Surah Al-Araf Ayah #23 Translated in Yoruba
قَالَا رَبَّنَا ظَلَمْنَا أَنْفُسَنَا وَإِنْ لَمْ تَغْفِرْ لَنَا وَتَرْحَمْنَا لَنَكُونَنَّ مِنَ الْخَاسِرِينَ
Awon mejeeji so pe: "Oluwa wa, a ti sabosi si emi wa. Ti O o ba forijin wa, ki O si ke wa, dajudaju a maa wa ninu awon eni ofo." gege bi won tun se gbagbo pe eje Anabi ‘Isa omo Moryam (’alaehi-ssolatu wa-ssalam) lori igi agbelebuu ti pa awon ese miiran re fun gbogbo awon t’o gbagbo ninu Jesu Kristi ati eje re lori igi agbelebuu. Allahu si so pe eleru-ese kan ko nii ru eru-ese elomiiran mo tire. Ikerin; awon kristieni di olusina nipa bi won se so Anabi ‘Isa omo Moryam ati iya re di olohun ti won n josin fun nitori pe won gba pe ikini keji won nikan ni ko ni egun ese eso jije lorun ati pe won tun gbagbo pe Hawa’ (rodiyallahu anha) je eso igi naa. Jije re si je ese lorun awon mejeeji nikan ko si ese eso jije lorun awon omo won kan kan. Koko keji: awon mejeeji toro aforijin lori asise naa ti won si so gbogbo omo re di elese eso nipase re ohun ni pe
Choose other languages:

Albanian

Amharic

Azerbaijani

Bengali

Bosnian

Bulgarian

Burmese

Chinese

Danish

Dutch

English

Farsi

Filipino

French

Fulah

German

Gujarati

Hausa

Hindi

Indonesian

Italian

Japanese

Jawa

Kazakh

Khmer

Korean

Kurdish

Kyrgyz

Malay

Malayalam

Norwegian

Pashto

Persian

Polish

Portuguese

Punjabi

Russian

Sindhi

Sinhalese

Somali

Spanish

Swahili

Swedish

Tajik

Tamil

Tatar

Telugu

Thai

Turkish

Urdu

Uyghur

Uzbek

Vietnamese

Yoruba
